Isaiah 30
1“Ègbé ni àwọn ọmọ fún orílẹ̀-èdè alágídí,” Olúwa wí, 2tí wọ́n lọ sí Ejibiti 3Ṣùgbọ́n ààbò Farao yóò jásí ìtìjú fún un yín, 4Bí àwọn olórí rẹ tilẹ̀ wà ní Ṣoani, 5gbogbo wọn ni a ó dójútì, 6Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ sí àwọn ẹranko tí ó wà ní gúúsù. 7sí Ejibiti tí ìrànlọ́wọ́ rẹ̀ 8Lọ nísinsin yìí, kí o sì kọ ọ́ sí ara wàláà fún wọn, 9Àwọn wọ̀nyí jẹ́ ọlọ̀tẹ̀ ènìyàn Olúwa. 10Wọ́n sọ fún àwọn aríran pé, 11Ẹ fi ọ̀nà yìí sílẹ̀, 12Nítorí náà, èyí ni ohun tí Ẹni Mímọ́ Israẹli wí: 13ẹ̀ṣẹ̀ yìí yóò rí fún ọ 14Yóò sì fọ́ ọ sí wẹ́wẹ́ bí àpáàdì 15Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè, Ẹni Mímọ́ ti Israẹli wí: 16Ẹ̀yin wí pé, ‘Bẹ́ẹ̀ kọ́, àwa yóò sálọ lórí ẹṣin.’ 17Ẹgbẹ̀rún (1,000) yóò sá 18Síbẹ̀síbẹ̀ Olúwa sì fẹ́ síjú àánú wò ọ́; Olúwa jẹ́ Ọlọ́run ìdájọ́. 19Ẹ̀yin ènìyàn Sioni, tí ń gbé ní Jerusalẹmu, ìwọ kì yóò sọkún mọ́. Báwo ni àánú rẹ̀ yóò ti pọ̀ tó nígbà tí ìwọ bá kígbe fún ìrànlọ́wọ́! Bí ó bá ti gbọ́, òun yóò dá ọ lóhùn. 20Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Olúwa fún ọ ní àkàrà ìyà àti omi ìpọ́njú, àwọn olùkọ́ rẹ kì yóò fi ara sin mọ́; pẹ̀lú ojú rẹ ni ìwọ ó rí wọn. 21Bí o bá yí sápá ọ̀tún tàbí apá òsì, etí rẹ yóò máa gbọ́ ohùn kan lẹ́yìn rẹ, wí pé, “Ọ̀nà nìyìí, máa rìn nínú rẹ̀.” 22Lẹ́yìn náà ni ẹ ó ba àwọn ère yín jẹ́ àwọn tí ẹ fi fàdákà bò àti àwọn ère tí ẹ fi wúrà bò pẹ̀lú, ẹ ó sọ wọ́n nù bí aṣọ tí obìnrin fi ṣe nǹkan oṣù ẹ ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ kúrò níbí!” 23Òun yóò sì rọ òjò fún un yín sí àwọn irúgbìn tí ẹ gbìn sórí ilẹ̀, oúnjẹ tí yóò ti ilẹ̀ náà wá yóò ní ọ̀rá yóò sì pọ̀. Ní ọjọ́ náà ni àwọn ẹran ọ̀sìn yín yóò máa jẹ koríko ní pápá oko tútù tí ó tẹ́jú. 24Àwọn màlúù àti àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí ó ń tú ilẹ̀ yóò jẹ oúnjẹ àdídùn tí a fi àmúga àti ṣọ́bìrì fọ́nkálẹ̀. 25Ní ọjọ́ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ yóò sọ ẹ̀mí wọn nù nígbà tí ilé ìṣọ́ yóò wó lulẹ̀, odò omi yóò sàn lórí òkè gíga àti lórí àwọn òkè kékeré. 26Òṣùpá yóò sì tàn bí oòrùn, àti ìtànṣán oòrùn yóò mọ́lẹ̀ ní ìlọ́po méje, gẹ́gẹ́ bí ìmọ́lẹ̀ odidi ọjọ́ méje, nígbà tí Olúwa yóò di ojú ọgbẹ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ tí yóò sì wo ọgbẹ́ tí ó ti dá sí wọn lára sàn. 27Kíyèsi i, orúkọ Olúwa ti òkèèrè wá 28Èémí rẹ̀ sì dàbí òjò alágbára, 29Ẹ̀yin ó sì kọrin Olúwa, 30Olúwa yóò jẹ́ kí wọn ó gbọ́ ohùn ògo rẹ̀ 31Ohùn Olúwa yóò fọ́ Asiria túútúú, 32Ẹgba kọ̀ọ̀kan tí Olúwa bá gbé lé wọn 33A ti tọ́jú Tofeti sílẹ̀ tipẹ́tipẹ́, Olúwa,