Psaumes 69
1Gbà mí, Ọlọ́run, 2Mo ń rì nínú irà jíjìn, 3Agara dá mi, mo ń pè fún ìrànlọ́wọ́; 4Àwọn tí ó kórìíra mi láìnídìí 5Ìwọ mọ òmùgọ̀ mi, Ọlọ́run; 6Má ṣe dójútì àwọn tí ó ní ìrètí nínú rẹ nítorí mi, Olúwa àwọn ọmọ-ogun; 7Nítorí rẹ ni mo ń ru ẹ̀gàn, 8Mo jẹ́ àjèjì si àwọn arákùnrin mi; 9nítorí ìtara ilé rẹ jẹ mí run, 10Nígbà tí mo sọkún 11nígbà tí mo wọ aṣọ àkísà, 12Àwọn tí ó jókòó ní ẹnu ibodè ń bú mi, 13Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti èmi ni Olúwa, 14Gbà mí kúrò nínú ẹrẹ̀, 15Má ṣe jẹ́ kí ìkún omi bò mí mọ́lẹ̀ 16Dá mí lóhùn, Olúwa, nínú ìṣeun ìfẹ́ rẹ; 17Má ṣe pa ojú rẹ mọ́ fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ: 18Súnmọ́ tòsí kí o sì gbà mí là; 19Ìwọ ti mọ ẹ̀gàn mi, ìtìjú mi àti àìlọ́lá; 20Ẹ̀gàn ba ọkàn mi jẹ́, 21Wọ́n fi òróró fún mi pẹ̀lú ohun jíjẹ mi, 22Jẹ́ kí tábìlì wọn kí ó di ìkẹ́kùn 23Kí ojú wọn kì í ó ṣókùnkùn, kí wọn má ṣe ríran, 24Tú ìbínú rẹ jáde sí wọn; 25Kí ibùjókòó wọn di ahoro; 26Nítorí wọ́n ń ṣe inúnibíni sí ẹni tí ìwọ ti lù, 27Fi ẹ̀sùn kún ẹ̀sùn wọn; 28Jẹ́ kí a yọ wọ́n kúrò nínú ìwé ìyè 29Ṣùgbọ́n tálákà àti ẹni-ìkáàánú ni èmí, 30Èmi yóò fi orin gbé orúkọ Ọlọ́run ga 31Eléyìí tẹ́ Olúwa lọ́rùn ju ọ̀dá màlúù lọ 32Àwọn òtòṣì yóò rí, wọn yóò sì yọ̀: 33Olúwa, gbọ́ ti aláìní, 34Kí ọ̀run àti ayé yìn ín, 35nítorí tí Ọlọ́run yóò gba Sioni là 36àwọn ọmọ ọmọ ọ̀dọ̀ ni yóò máa jogún rẹ̀,