Psaumes 39
1Mo wí pé, “Èmi yóò ṣọ́ ọ̀nà mi 2Mo fi ìdákẹ́ ya odi; 3Àyà mi gbóná ní inú mi. 4“Olúwa, jẹ́ kí èmi kí ó mọ òpin mi, 5Ìwọ ti ṣe ayé mi Sela. 6“Nítòótọ́ ni olúkúlùkù ń rìn kiri bí òjìji. 7“Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí, Olúwa, 8Gbà mí lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo. 9Mo dákẹ́ jẹ́ẹ́; 10Mú pàṣán rẹ kúrò ní ara mi; 11Ìwọ fi ìbáwí kìlọ̀ 12“Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa, 13Dá mi sí, kí èmi lè ní agbára,