YOR Psalmów Rozdział 4

Psalmów 4

YOR · Porównaj · Audio

1Dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́, 2Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, tí ẹ ó ṣe sọ ògo mi di ìtìjú? 3Ṣùgbọ́n kí ẹ mọ̀ pé, Olúwa ti ya ẹni olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀; Olúwa yóò gbọ́ nígbà tí mo bá pè é. 4Ẹ bínú ẹ má ṣe ṣẹ̀, 5Ẹ rú ẹbọ òdodo Olúwa. 6Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ń béèrè pé, “Ta ni yóò ṣe rere fún wa?” Olúwa, jẹ́ kí ojú rẹ mọ́lẹ̀ sí wa lára, 7Ìwọ ti fi ayọ̀ púpọ̀ kún ọkàn mi 8Èmi yóò dùbúlẹ̀, èmi ó sì sùn ní àlàáfíà, Olúwa,

Osiągnięto dzienny limit

Zmień plan na nowszy, aby kontynuować korzystanie z funkcji AI z wyższymi dziennymi limitami.

Porównaj wszystkie plany →