Psalmów 54
1Gbà mí, Ọlọ́run nípa orúkọ rẹ: 2Gbọ́ àdúrà mi, Ọlọ́run; 3Àwọn agbéraga àlejò dìde sí mí. 4Kíyèsi i Ọlọ́run ni olùrànlọ́wọ́ mi; 5Jẹ́ kí ibi padà sẹ́yìn sí àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ sí mi; 6Èmí yóò rú ẹbọ àtinúwá sí ọ, Olúwa, 7Nítorí tí ó yọ mí kúrò nínú ibi gbogbo