Psalmen 122
1Inú mi dùn nígbà tí wọ́n wí fún mi pé, Olúwa.” 2Ẹsẹ̀ wa yóò dúró ní ẹnu ibodè rẹ, 3Jerusalẹmu, ìwọ tí a kọ́ bí ìlú 4Níbi tí àwọn ẹ̀yà máa ń gòkè lọ, Olúwa, Olúwa. 5Nítorí ibẹ̀ ni a gbé ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀, 6Gbàdúrà fún àlàáfíà Jerusalẹmu; 7Kí àlàáfíà kí ó wà nínú odi rẹ̀, 8Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mi 9Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa,