Salmi 40
1Mo fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ dúró de Olúwa; 2Ó fà mí yọ gòkè 3Ó fi orin tuntun sí mi lẹ́nu, Olúwa. 4Ayọ̀ ni fún àwọn wọ̀n-ọn-nì Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé wọn 5Olúwa Ọlọ́run mi, 6Ẹbọ àti ẹran ẹbọ ni ìwọ kò fẹ́, 7Nígbà náà ni mo wí pé, 8Mo ní inú dídùn 9Èmi ti sọ ìròyìn ayọ̀ ti ìgbàlà Olúwa. 10Èmi kò fi ìrànlọ́wọ́ ìgbàlà sin ní àyà mi; 11Ìwọ má ṣe, fa àánú rẹ tí ó rọ́nú sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ mi Olúwa; 12Nítorí pé àìníye ibi 13Jẹ́ kí ó wù ọ́, Olúwa, Olúwa, 14Gbogbo àwọn wọ̀n-ọn-nì ni kí ojú kí ó tì 15Jẹ́ kí àwọn tí ó wí fún mi pé, “Háà! Háà!” 16Jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ń wá ọ Olúwa!” 17Bí ó ṣe ti èmi ni,