예레미야 4
1“Tí ìwọ yóò bá yí padà, ìwọ Israẹli, padà tọ̀ mí wá,” Olúwa wí. 2Tí ó bá jẹ́ lóòtítọ́ àti òdodo ni ìwọ búra. Olúwa ti wà láààyè, 3Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu: 4Kọ ara rẹ ní ilà sí Olúwa, 5“Kéde ní Juda, kí o sì polongo ní Jerusalẹmu, kí o sì wí pé: 6Fi àmì láti sálọ sí Sioni hàn, 7Kìnnìún ti sá jáde láti inú ibùgbé rẹ̀, 8Nítorí náà, gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀ Olúwa 9“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí pé, 10Nígbà náà ni mo sì wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè, báwo ni ìwọ ti ṣe tan àwọn ènìyàn wọ̀nyí àti Jerusalẹmu jẹ nípa sísọ wí pé, ‘Ìwọ yóò wà ní àlàáfíà,’ nígbà tí o jẹ́ wí pé idà wà ní ọ̀fun wa.” 11Nígbà náà ni a ó sọ fún Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn pé, “Ẹ̀fúùfù líle láti aṣálẹ̀ fẹ́ lu àwọn ènìyàn mi, kì í ṣe láti sọ di mímọ́. 12Ẹ̀fúùfù líle tí ó wá láti ọ̀dọ̀ mi. Báyìí mo kéde ìdájọ́ mi lórí wọn.” 13Wò ó! O ń bọ̀ bí ìkùùkuu 14Ìwọ Jerusalẹmu, mú búburú kúrò lọ́kàn rẹ kí o sì yè. 15Ohùn kan sì ń kéde ní Dani 16“Sọ èyí fún àwọn orílẹ̀-èdè, 17Wọ́n yí i ká bí ìgbà tí àwọn ọkùnrin bá ń ṣọ́ pápá, Olúwa wí. 18“Ìwà rẹ àti ìṣe rẹ 19Háà! Ìrora mi, ìrora mi! 20Ìparun ń gorí ìparun; 21Yóò ti pẹ́ tó, tí èmi yóò rí ogun 22“Aṣiwèrè ni àwọn ènìyàn mi; 23Mo bojú wo ayé, 24Mo wo àwọn òkè ńlá, 25Mo wò yíká n kò rí ẹnìkan; 26Mo bojú wò, ilẹ̀ eléso, ó sì di aṣálẹ̀ Olúwa àti níwájú ríru ìbínú rẹ̀. 27Èyí ni ohun tí Olúwa wí: 28Nítorí náà, ayé yóò pohùnréré ẹkún 29Nípa ariwo àwọn ẹlẹ́ṣin àti àwọn tafàtafà 30Kí ni ò ń ṣe, ìwọ tí o ti di ìjẹ tán? 31Mo gbọ́ ìró kan bí i igbe obìnrin tó ń rọbí,